Awùjalẹ̀̀ ni orúkọ oyè Ọba ìbílẹ̀ Ìjẹ̀bú. Ẹni tó bá wà ní ipò yìí ni wọ́n ń pè ní Awùjalẹ̀ ti Ìjẹ̀bú.[1] Awùjalẹ̀ tó wà lórí oyè lọ́wọ́lọ́wọ́ ni Ọba Sikiru Kayode Adetona Ògbágbá Kejì, tí ó wá láti ìdílé Anikinaiya.
Nínú ìwé òfin ti àwọn lọ́balọ́ba tó ń ṣàkóso ìlú Ìjẹ̀bú, àwọn ìdílé Ọlọ́ba mẹ́rin ni ó wà:[2]
Ọjọ́ kìíní oṣù kẹsàn-án ọdún 1959 ni wọ́n fi èyí lélẹ̀.
|url-status=
ignored (help)
|url-status=
ignored (help)
© MMXXIII Rich X Search. We shall prevail. All rights reserved. Rich X Search